a
Lk 6.17
,
20-23
;
Mk 3.13
;
Jh 6.3
.
Matthew 5:1-2
Ìwàásù orí òkè
1
a
Nígbà tí ó rí ọ̀pọ̀ ènìyàn, ó gun orí òkè lọ ó sì jókòó. Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ si tọ̀ ọ́ wá.
2
Ó sì bẹ̀rẹ̀ sí kọ́ wọn.
Ó wí pé:
Copyright information for
YorBMYO